Iyán Ogún Ọdún láti ọwọ́ọ Oyèwọlé Ògúnwálé
Iyán Ogún Ọdún is a Yoruba play set in the town of Ọ̀ṣun where the respected chieftaincy title of Balógun is left vacant.
Drama section explores landmark Yoruba plays and theatrical works. This section profiles playwrights, scripts, performance histories, and structural features central to Yoruba stage literature.
Iyán Ogún Ọdún is a Yoruba play set in the town of Ọ̀ṣun where the respected chieftaincy title of Balógun is left vacant.
In this post, we shall examine the summary of Eégún Aláré by Láwuyì Ògúnníran; the story of Ọ̀jẹ́làdé, a humorous masquerader.
Ẹfúnṣetán Aníwúrà, Ìyálóde of Ìbàdàn is a play written by Akínwùmí Ìṣọ̀lá and published by University Press PLC in 1970.
Baba Igbomina by Tolani Awotayo is a didactic play published by MAMSA Publishers in 2006 about the importance of hard work.
Eégún Aláré jẹ́ ìwé ìtàn àròsọ tó sọ ìtàn Ọ̀jẹ́làdé, to jẹ́ eégún aláré, àti àwọn itú tó pa. Olóògbé Láwuyì Ògúnníran ni ó kọ ìwé náà.
Ẹfúnṣetán Aníwúrà, Ìyálóde Ìbàdàn jẹ́ eré oníṣe láti ọwọ́ọ Akínwùmí Ìṣọ̀lá tí University Press PLC tẹ̀ jáde ní ọdún 1970.
Bàbá Ìgbómìnà jẹ́ eré oníṣe láti ọwọ́ọ Tọ́lání Awótáyọ̀ tí ilé iṣẹ́ ìtẹ̀wé MAMSA Publishers tẹ̀ jáde lọ́dún 2006. Ìwé náà ṣàfihàn pàtàkì ìmúra ṣíṣẹ́ àti bí ó ṣe jẹ́ pé kò sí ẹnì tó mọ ọ̀la.