A Review of Ìjàpá Tìrókò Ọkọ Yánníbo by Ọlágòkè Òjó
Ìjàpá Tìrókò Ọkọ Yánníbo is a collection of twenty short folktales by Ọlágòkè Òjó, first published by Learn Africa Plc in 1973.
Ìjàpá Tìrókò Ọkọ Yánníbo is a collection of twenty short folktales by Ọlágòkè Òjó, first published by Learn Africa Plc in 1973.
Ẹfúnṣetán Aníwúrà, Ìyálóde of Ìbàdàn is a play written by Akínwùmí Ìṣọ̀lá and published by University Press PLC in 1970.
Baba Igbomina by Tolani Awotayo is a didactic play published by MAMSA Publishers in 2006 about the importance of hard work.
Ìjàpá Tìrókò Ọkọ Yánníbo jẹ́ àkójọpọ̀ ogún ìtàn àròsọ kéékèèké tó wá láti ọwọ́ọ Ọlágòkè Òjó, tí Learn Africa Plc sí kọ́kọ́ gbé jáde ní ọdún un 1973.
Eégún Aláré jẹ́ ìwé ìtàn àròsọ tó sọ ìtàn Ọ̀jẹ́làdé, to jẹ́ eégún aláré, àti àwọn itú tó pa. Olóògbé Láwuyì Ògúnníran ni ó kọ ìwé náà.
Ẹfúnṣetán Aníwúrà, Ìyálóde Ìbàdàn jẹ́ eré oníṣe láti ọwọ́ọ Akínwùmí Ìṣọ̀lá tí University Press PLC tẹ̀ jáde ní ọdún 1970.
Bàbá Ìgbómìnà jẹ́ eré oníṣe láti ọwọ́ọ Tọ́lání Awótáyọ̀ tí ilé iṣẹ́ ìtẹ̀wé MAMSA Publishers tẹ̀ jáde lọ́dún 2006. Ìwé náà ṣàfihàn pàtàkì ìmúra ṣíṣẹ́ àti bí ó ṣe jẹ́ pé kò sí ẹnì tó mọ ọ̀la.